Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Ẹ má bá àwọn iléeṣẹ́ 58 yìí dòwòpọ̀, wọ́n yóò lù yín ní jìbìtì – EFCC kìlọ̀
EFCC lo fi orukọ awọn ileeṣẹ naa lede ninu atẹjade kan loju opo ayelujara rẹ.

Lassa Fiver gba ẹ̀mí dókítà kan nípìnlẹ́ Ondo
Bi iṣẹlẹ naa se waye ni ọpọ iwadii ti bẹrẹ lori lati dena aisan yii lawujọ ni orilẹede Naijiria ati ni ilẹ UK.

Àwọn ọlọ́jà àti iléeṣẹ́ panápaná ń sọ̀kò ọ̀rọ̀ síra wọn lórí ọjà Aleshinloye tó jóná n'Ibadan
Ni aṣalẹ, ọjọ kọkanla oṣu kẹta ọdun 2025 ni ina sẹyọ ninu Ọja Aleshinloye, ti ọpọ nnkan ọja to le ni ọpọ milọnu si jona kọja idanimọ.

Ọ̀rọ̀ Sunday Igboho àti ìjọba àpapọ̀ gba ọ̀nà míràn yọ; Igboho tún ẹjọ́ pè
Ọrọ ọjọ ti Sunday Igboho pe ijọba apapọ Naijiria lori bi awọn oṣiṣẹ alaabo DSS ṣe kọlu ile rẹ tun ti ba ibomiran yọ.

'Ibi iṣẹ́ òòjọ́ ni ọ̀rẹ́ mi lọ ti àkìtan fi wó pa á'
Iṣẹ oojọ ni ọdọkunrin kan, Sanya Kezia, ẹni ọdun mọkanlelogun,(21), wa lọ si ori akitan ti wọn n da idọti si lorilẹede Uganda, nibẹ ni òketè ilẹ naa si ti ya bo o mọlẹ, to ṣe bẹẹ ku.

Kò ṣeé má gbọ̀ọ́
Kò ṣeé má gbọ̀ọ́

Ẹ̀mí ṣòfò, èèyàn mẹ́rin farapa, ọ̀pọ̀ dúkìá jóná nínú ìjàmbá iná lórí afárá Otedola l'Eko
Ileeṣẹ to n ri si iṣẹlẹ pajawiri l'Eko, LASEMA lo fidi iroyin naa mulẹ ninu atẹjade to fi ṣọwọ si awọn akọroyin.

Natasha Akpoti gbé ẹjọ́ Akpabio àti àwọn aṣofìn yòókù lọ sí àjọ àwọn obìnrin l'ágbàyé
Aṣofin to n ṣoju Aarin-gbungbun ipinlẹ Kogi ṣaaju idaduro rẹ naa n beere fun idasi ajọ Iṣokan Agbaye lati gbeja rẹ ja lori ẹsun fifi ilọlukọ lọ ọ lọna ifẹ, to ni Godswill Akpabio, olori ile igbimọ aṣofin agba ni Naijiria fi lọ oun.

Ibí yìí ni Ọya wọlẹ̀ sí nílùú Ira, ìpínlẹ̀ Kwara, àti ìdí gan-an tó fi bínú wọlẹ̀
BBC ṣe àbẹ̀wò sí ibi tí Òrìṣà Ọya wọlẹ̀ sí nílùú Ira, ìpínlẹ̀ Kwara. Àwọn nnkan tí a rí níbẹ̀ rèé

Wo ìdí tí àwọn aṣòfin ṣe ní kí NCC fòfin de ojú òpó tó ń sàfihàn ìbálòpọ
Tafoki ni awọn fọnran ibalopọ lo jẹ aisan agbaye, ti Naijiria si kọ lati gbe igbesẹ to yẹ lati tako iwa yii lawujọ.

Amẹrika ṣètò áàpù fún àwọn tí kò ní ìwé ìgbélùú, tó sì fẹ́ ẹ̀ já padà s'orílẹ̀èdè wọn
Ṣaaju ni ijọba Amẹrika ti kọkọ ke si awọn eeyan ti ko ni iwe igbelu nibẹ lati maa fi ilẹ naa silẹ funra wọn lai ṣe pe oun fi tipa tikuuku le wọn kuro nibẹ.

Obìnrin kan déèrò ẹ̀wọ̀n lẹ́yìn tó sọ fún Jesu pé kó gé irun orí rẹ̀ lórí Tiktok
Igbẹjọ rẹ lo waye lẹyin ti oniruru ẹgbẹ awọn ọmọlẹyin Kristi kọwe ẹsun ọrọ odi mọ afurasi ọhun.

Mọ̀ nípa ààrùn Diphtheria tó pa akẹ́kọ̀ọ́ kan, sọ ọ̀pọ̀ di èèrò iléèwòsàn l'Eko
Arun ti oloyinbo n pe ni Diphtheria jẹ arun kan to maa n tete ràn gidi.

Bí o ṣe lè dá ayédèrú kọ́ndọ́mù mọ̀ lórí igbá
Ninu fidio kan to gba ori ayelujara, ajọ NAFDAC sọ pe ayederu ni gbogbo rọba idaabobo "Kiss" to wa ninu ọja.

'Géètì ni ọkọ mi ní kí n wá á ṣí fún òun, à ṣé àwọn tí yòó paá ti wà lẹ́nu ọ̀nà'
Ni ọjọ Kẹwaa, ọjọ Aje ni BBC News Yoruba sabẹwo si ile oloogbe naa nibiti ọpọ eeyan darijọ si lati sedaro ẹni wọn to lọ.

Ilé ẹjọ́ fún Oriyomi Hamzat àti olorì Naomi ní ọ̀nà àbáyọ láti tètè yanjú ìgbẹ́jọ́ wọn
Ti ẹ ko ba gbagbe ọmọde marundinlogoji lo ku nibi eto ti wọn gbe kalẹ lati ṣe iranwọ fun awọn to ku diẹ kaato fun lawujọ ni ipari ọdun 2024.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Ọdún márùn-ún lẹ́yìn àjàkálẹ̀ Corona: Ẹ̀kọ́ mẹ́rin tó kọ́ wa
Ajọ Iṣọkan Agbaye si ti sọ pe iku to waye lati ara Corona bayii ti wọ miliọnu mẹẹẹdogun.

Bó ṣe yẹ́ kí o máa kírun òru nínú Ramadan àti pàtàkì rẹ̀
Koda, ọrọ ẹnu Anabi Muhammed (Ki ikẹ ati ọlà Oluwa maa ba a) ti a mọ si Hadith, gba awọn Musulumi niyanju lati maa ji loru kirun, ki wọn beere ohun ti wọn ba n fẹ lọdọ Ọba Allah.

Bí ilé ẹjọ́ ṣe kọ́kọ́ yọ mi nípò Eleruwa, jẹ́ kí n gbóòrùn ara mi - Eleruwa
Oba Samuel Adebayo Adegbola sọrọ lori bi ijọba ṣe daa pada sipo ọba gẹgẹ bi Eleruwa, lẹyin ọdun mẹfa ti ile-ẹjọ kọkọ yọ ọ.

Wọ́n yẹgi fún ọmọ ọ̀dọ̀ lórí ẹ̀sùn pé o pa ọmọ ọ̀gá rẹ̀ tó ń tọ́jú
Inu oṣu Keje ọdun 2023 ni wọn ṣedajọ iku fun, ti ile ẹjọ si kọ ẹjọ kotẹmilọrun to pe ninu oṣu Keji, ọdun 2024.

Nasir El-Rufai fi ẹgbẹ́ òṣèlú APC sílẹ̀, ó darapọ̀ mọ́ SDP
El-Rufai kede eyi ninu atẹjade kan to fi sita lọjọ Aje, Ọjọ kẹwaa oṣu kẹta ọdun 2025, o ni ẹgbẹ oṣelu ti yabara kuro ninu ida pataki ti wọn fi da silẹ lọdun 2013.

"Ẹbí fi mí yáwó nítorí àìsàn, ni mo ṣe di ẹrú lóko igbó''
Gẹgẹ bi alaye , nigba ti Baba Nam ni arun jẹjẹrẹ ẹdọforo, awọn ẹbi rẹ ya owo tiye rẹ jẹ £186,564 lọwọ olowo ele kan.

DR Congo kéde ẹ̀bùn $5m fún ẹnikẹ́ni tó bá báwọn mú olórí ọmọ ogun ọlọ̀tẹ̀
Ní ọdún tó kọjá, ilé ẹjọ́ tó ń rí sí ọ̀rọ̀ àwọn ológún ṣe ìdájọ́ àwọn ọkpunrin mẹ́tẹ̀ẹ̀ta náà láì sí wón níbẹ̀, tí ilé ẹjọ́ náà sì dájọ́ ikú fún wọn fẹ́sùn ìdìtẹ̀ mọ́ ìjọba.

Ohun mẹ́sàn-án nípa Lesotho, orílẹ̀èdè tí 'ẹnìkan kò gbúròó rẹ̀ rí'
Orilẹede kekere to wa ni Guusu ilẹ Africa ni Lesotho. O kun fun awọn oke, orilẹede South Africa lo si yi i ka porogodo.

Afurasí yìnbọn pa alákòso WhatsApp nítorí tó yọ ọ́ lórí ìkànnì náà
Wọ́n ní Ashfaq àti Mushtaq ní ìfaǹfà lórí ìkànnì WhatsApp kan tí àwọn méjéèjì jọ wà èyí tó mú kí Mushtaq yọ Ashfaq lórí ìkànnì náà.

Aláàfin Oyo, Ọba AbdulAkeem Owoade bẹ̀rẹ̀ orò ìpèbí lẹ́yìn oṣù kan tó gba ọ̀pá àṣẹ
Olórí òṣìṣẹ́ sí Aláàfin tuntun náà, Rotimi Osuntola ló kéde èyí nínú àtẹ̀jáde kan tó fi léde lọ́jọ́ Ẹtì.

Wo nǹkan mẹ́rin tó lè fa ikú òjijì fún èèyàn
Iku ko kan ọjọ ori, nitori ọmọ ọwọ n ku, bẹẹ ni ọdọ langba ti nnkan ko ṣe naa a maa ku lojiji.

Wo bí àwọn obiǹrin yìí ṣe dáhùn ìbéèrè láyàájọ́ àwọn obìnrin lágbàáyé fún 2025
Idahun awọn ibeere lori awọn akọni obinrin lorilẹede Naijiia, bi a ṣe n ṣe ajọyọ ayajọ awọn obinrin lagbaaye lonii, ọjọ kẹjọ, oṣu Kẹta ọdun 2025.

Kìí ṣe nítorí ẹ̀sùn ìbálòpọ̀ ni a ṣe ní kí Natasha lọ rọ́kún nílé, àwọn ẹ̀ṣẹ̀ márùn-ún tó ṣẹ̀ nìyí - Ilé aṣòfin
Bamidele nínú àtẹ̀jáde náà sọ pé àwọn ìwà àìtọ́ tí Natasha hù sílé aṣòfin ló fa ìjìyà tí ilé aṣòfin fún un.

Agbébọn yìnbọn mọ́ bààlúù UN, èèyàn mẹ́tàdínlọ́gbọ̀n kú
Gẹgẹ bi UN ṣe wi, wọn ni ikọlu yii le pada di ogun.

Ìdí rèé tí ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ fi lé Eleruwa, Ọba Adebayo Adegbola kúrò lórí ìtẹ́, kí Makinde tó yàn-án padà lẹ́yìn ọdún mẹ́fà
BBC Yoruba tu itan wo yẹbẹyẹbẹ lati ran wa leti awọn koko ẹsun ti ile ẹjọ kotẹmilọrun we mọ Ọba Adegbola lọrun lọdun 2019, to fi ni ko yẹ lori itẹ Eleruwa.

Wo àwọn ọba alayé tí wọ́n gba adé lórí wọn ní Nàíjíríà
BBC Yoruba ti wa mu diẹ lara awọn ọba alaye ti ijọba tabi igbimọ to n ri sọrọ ọba lawọn ilu kọọkan ni Naijiria ti rọ nipo.

Àkọsílẹ̀ iye èèyàn tó bá ìkọlù agbébọn lọ ni 2024 rèé àti ipò tí Nàíjíríà wà nínú ìgbésùnmọ̀mí
Ẹka Global Terrorism Index ṣalaye pe Naijiria ti sun kuro ni ipo kẹjọ to wa ni 2023 ati 2024, pẹlu alekun to ba odiwọn iwa ipá to waye, to ti goke di bayii.

Mi ò lórí ọkọ, mo lé lọ́gbọ̀n ọdún, kò sọ́kọ, kò sọ́mọ, mo fẹ́ ṣẹ́yún tí mo pàpà ní torí ẹni tó fún mi lóyún kò gbà á -Wasila Coded
Bimpe Akintunde ni oun fẹ ṣẹ oyun to ti ga sita, nitori ọkunrin toun loyun naa fun ko gba a rara, diẹ lo ku ki oun ba oyun naa lọ.

Wo bí ìgbẹ́jọ́ Alfa Abdurahman, afurasí tí wọ́n bá òkú Yetunde nílé rẹ̀ n'Ilorin, ṣe lọ lónìí
Igbẹjọ naa waye ni ile ẹjọ Majisireeti to wa ni idojukọ ile ẹjọ giga ipinlẹ Kwara niluu Ilorin .

Kí ló dé táwọn sọ́jà yabo àwọn òṣìṣẹ́ amúnáwá ní Ikeja, lù wọ́n lálùbami, tí wọn fi ń fo ògiri jáde lọ́ọ́fìsì?
Ni nnkan bii ago mẹjọ ku ogun iṣẹju ni a gbọ pe awọn sọja naa ya wọ olu ileeṣẹ apinaka IKEDC ti ko jina si ileeṣẹ ijọba ipinlẹ Eko ni Ikeja.

Ẹ̀rọ ló gé mi lọ́wọ́ lẹ́nu iṣẹ́ tí mo fi di ọlọ́wọ́ kan tó ń fi Gángan yin Ọlọ́run - Ayomide Moses
Ayomide Moses ni awọn ẹya ara rẹ pe perepere nibẹrẹ aye rẹ amọ lẹyin to pari iwe mẹwa ni isẹlẹ nla sẹlẹ, eyi to mu ọwọ rẹ kan lọ.

Àìsàn ẹ̀jẹ̀ rúru ló kọ́ ṣe 'I Sho Pepper'', ó ń pọ̀ ẹ̀jẹ̀ lórí ahọ́n, dákú fọ́jọ́ mẹ́sàn -án, kí ọlọ́jọ́ tó dé - Yetunde Ogunsola
Ọdun 1972 ni Yetunde Ogunsola to jẹ ọmọbibi ilu Ilesha bẹrẹ ere tita lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ oṣere oloogbe ''I Sho Pepper.''

Wo àwọn àìsàn tó le ṣúyọ ní àgọ́ ara lásìkò ààwẹ̀
Lásìkò àwẹ̀, àwọn ènìyàn máa ń séra fún oúnjẹ jíjẹ, omi mímu àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ àmọ́ ẹ wo àwọn àrùn tó le ti ìdí ààwẹ̀ súyọ.

Local Housing

This is one of the main issues facing local people. The inadequacy of social housing stock continues to be the main concerns of local people. And it is getting worst.

Read More

Drugs And Illegal Substances

Taking illegal drug is always fraught with danger. You don't need me to tell you that - your grand mother will say the same. The high very often tend to perpetual low that you will never get out from. Get advise now before it is too late

Read More

Knife Attacks

Who goes around with a knive as weapon of protection is deluded. It will inevitably be your comeuppance. Just in case you do not understand, it will kill you. There is no justification for carrying a knive excerpt when you are foraging in the jungle.

Read More

Gang Culture

We were all young once - doing things adults will frown upon. This was at school or in the play grounds. But as we grew up, people we wanted to associate with start to shrink in numbers as our brain matured correspondingly and as a result doing the right thing. Pick your friends judiciously.

Read More

Local Parks

From a personal experience - the local park is a refuge for meditation,physical exploration and mental rejuvination. Just go for a slow run and see how you feel afterwards. Physical and mentally rewarding. Don't just take my words for it - it is a scientific fact. Please do try it.

Read More

24/7 Support

We are your one stop local solution advocate. Dont't carry all that weight on your own we are here to not only relief some of it, but to help you get back to you again.

Read More
Established since 2000

We Are Ready To Assist