Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Ilé aṣòfin bẹ̀rẹ̀ ìgbésẹ̀ láti sọ Aláàfin di alága ìgbìmọ̀ lọ́balọ́ba l‘Oyo, Olubadan ni igbákejì, Soun ni igbá kẹta, Olubadan bá yarí
Saaju ninu iwe ofin lọbalọba ti ọdun 2000, Alaafin ni olori lọbalọba nipinlẹ Oyo, pẹlu aṣẹ lati ọwọ ijọba lati dari ipade ati awọn nnkan mii .

"Ọgbẹ́ ọkàn ló jẹ́ pé Faith, ọmọ mi pa ara rẹ̀ tórí ó gba máàkì kékeré nínú èsì ìdánwò JAMB"
Opesusi Oluwafemi, tíí ṣe bàbá Faith, ọmọbìnrin tó pa ara rẹ̀ torí máàkì kékeré tó gbà nínú èsì ìdánwò JAMB, bá BBC sọ̀rọ̀ nípa bí ìṣẹ̀lẹ̀ náà ṣe wáyé, irú èèyàn tí ọmọ rẹ̀ jẹ́ àti ipò ìbànújẹ́ tó ẹbí rẹ̀ wà.

Kí ló mú kí ìjọba Kwara gbé ilé ẹ̀kọ́ girama méjì tipa n'Ilorin?
Kọmisona feto ẹkọ ni ipinlẹ Kwara, Ọgbẹni Ọlọhungbẹbẹ Lawal, ṣalaye ninu atẹjade kan to fi sita pe ijọba ti awọn ile ẹkọ naa latari aawọ to bẹ silẹ laarin awọn akẹkọọ lati ile ẹkọ mejeeji.

Ọdún Egúngún àgbáyé sọkutu wọ̀wọ̀ nílùú Ibadan, àlàyé rèé lórí ìsesí egúngún pàtàkì mẹ́wàá tó pitú
Jakejado orilẹede Naijiria ati ilẹ okere ni ọpọ aṣoju awọn idile ti wọn ti n gbe awọn Egungun ti peju pesẹ, fun ajọyọ t'ọdun yii.

"Ìyàwó àti ọmọ mi márùn-ún kú lọ́jọ́ kan ṣoṣo lẹ́yìn tí wọ́n jẹ ìrẹsì tán"
Ọkunrin naa, Arinze Robinson Ahalu, ṣalaye ninu ifọrọwanilẹnuwo to ṣe pẹlu BBC pe irẹsi lawọn ọmọ oun ati iyawo jẹ lọjọ naa, ti wọn si gba ibẹ ku.

Jumoke George tí mọ ibi tí ọmọ rẹ̀ àmọ́ nǹkan kò fara rọ fún-un níbẹ̀ - Biola Bayo
Nínú fọ́nrán ohùn àti àwòrán kan tó gba orí ayélujára, ni gbajúmọ̀ òṣèré tíátà, Jumoke George pẹlu omije loju ṣalaye pe, ọdun kẹrin ree ti ọmọ rẹ obinrin ti di awati, to si tun da ọmọ meji silẹ fun oun lati maa tọju wọn.

Àwọn akẹ́kọ̀ọ́ àtàwọn òbí fẹ́ kí àjọ JAMB fagilé gbogbo èsì ìdánwò UTME tó jáde torí àṣìṣe tó wà níbẹ̀
Awọn eeyan yii tako igbesẹ ajọ JAMB lati tun idanwo naa ṣe nipinlẹ Eko ati lawọn ipinlẹ ẹkun ila oorun guusu Naijiria nikan.

Ìdí tí Tinubu ṣe fi òfin de kíkó àwọn ọjà kan wọlé sí Nàíjíríà láti ilẹ̀ òkèèrè
Aarẹ Tinubu tun sọ gbedeke iye awọn akọṣẹmọṣẹ ilẹ okeere to le wọ Naijiria lati wa ṣiṣẹ tawọn ọmọ Naijiria naa le ṣe funra wọn.

Ohun tí a mọ̀ rèé nípa ‘ìrẹsì olóró’ tí wọ́n ló wọ ìpínlẹ̀ Ogun àti Eko
Gẹgẹ bi awọn to n pin ikilọ naa ka ṣe wi ninu awọn fọnran ohun wọn, oniṣowo kan ni wọn lo fi Ògún ṣepe nitori irẹsi rẹ ti wọn ji ko wọ Naijiria.

Wo bí ìmọ̀ ẹ̀rọ àtọwọ́dá àti àsọdùn ṣe ń gbóríyìn fún olórí ológun
O le lọgọrun-un fidio bayii ti wọn lo imọ ẹrọ ti a mọ si AI ṣe, eyi to n ṣafihan Traoré bii akọni ọmọ ilẹ Afrika, ọpọ rẹ lo jẹ pe oun ti ko ri bẹẹ ni wọn n sọ. Ọpọlọpọ fidio bayii lo ti kun ori ayelujara kaakiri ẹkun Sahara ilẹ Africa lati ipari oṣu Kẹrin.

"Àwọn ológun wà níbí lóòótọ́, ṣùgbọ́n kò sí ààbò fún wa"
Ero awọn eeyan tẹlẹ ni pe ologun Naijiria pẹlu ajọṣepọ awọn orilẹede alamuleti, ti ṣẹgun Boko Haram, ṣugbọn ni bayii, ikọlu naa n waye leralera lati nnkan bii ọdun mẹta sẹyin.

Wo eré tíátà mẹ́wàá tó sọ fíìmù Yorùbá di ìlúmọ̀ọ́ká ní àgbáyé
BBC Yorùbá ṣe àkójọpọ̀ àwọn eré tíátà mẹ́wàá ní èdè Yorùbá tí wọn gbé jáde lọ́pọ̀ ọdún sẹ́yìn, èyí tó ṣe àfihàn àṣà àti ìṣe wa fún gbogbo àgbáyé.

Kí ló ń fa ìwà ìṣekúpa ẹnìkejì ẹni tó ń wáyé lójúmọ̀ ní Naijiria?
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa Kano, SP Abdullahi Haruna Kiyawa ni iṣẹlẹ naa waye ni agbegbe Faraw ni ijọba Tarauni nipinlẹ Kano.

"Ojú ọ̀nà Ikare sí Ogbagi di pàkúté ikú, ẹ̀mí arìnrìnàjò ń bọ́ púpọ̀ torí ìjàmbá ọkọ̀, ìkọlù adigunjalè àtàwọn ajínigbé"
BBC Yorùbá ṣe àbẹ̀wò sí ojú ọ̀nà Ikare si Ogbagi níbi tí ìjàmbá ọkọ̀, adigunjalè àtàwọn ajínigbé ti ń gba ẹ̀mí ọ̀pọ̀ arìnrìnàjò láìníye.

Lẹ́yìn iṣẹ́ abẹ kejì ní ikùn rẹ̀, Taiwo Awoniyi jí sáyé padà, ó kúrò ní ẹsẹ̀ kan ayé, ẹsẹ̀ kan ọ̀run
Awoniyi ni wọn gbe digbadigba lọ ile iwosan ni ọjọ Aje, lẹyin to kọlu opo oju ile bọọlu lori paapa nigba ti ikọ agbabọọlu rẹ n koju ikọ Leicester City lọjọ Aiku to kọja.

Ìyàwó ilé tó di ògbóǹtarìgì nínú ìdíje àgbáyé fáwọn èèyàn tó sán eegun
Igbe aye Roya n sọ nipa obinrin ti aṣa da lọwọ kọ amọ ti o ti dominira, to si jẹ awokọṣe fawọn obinrin ẹgbẹ rẹ.

Darapọ̀ mọ́ wa lórí WhatsApp
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ

Wọ́n ti sin àgékù ara Hafsot Lawal tí afurasí Abdulrahman gé wẹ́lẹ́wẹ́lẹ́ n'Ilorin
Nnkan bi aago mẹrin irọlẹ ọjọ isẹgun ni wọn ṣin oku oloogbe naa ni itẹ́ isinku awọn musulumi to wa ni agbegbe Sango niluu Ilọrin.

Kí ni yóò ṣẹlẹ̀ s'áwọn akẹ́kọ̀ọ́ bí JAMB ṣe l'óun yóò ṣe àtúnyẹ̀wò èsì ìdánwo 2025?
Esi idanwo naa ti a mọ si 'Unified Tertiary Matriculation Examination' (UTME) ni wọn fi lede lọjọ Ẹti to kọja, ti awọn to kuna si pọ lọ jara.

Ọwọ́ NDLEA tẹ obìnrin tó gbé òògùn olóró pamọ́ sójú ara rẹ̀ lọ sí Iran
Bi NDLEA ṣe wi, hijaabu ti awọn obinrin Musulumi maa n wọ ni Obehi wọ lati bo aṣiri ara rẹ ki wọn ma baa mu un.

'Ọ̀pọ̀ ọdún ni ọkọ mi fi lòògùn oorun fún mi kó lè baà ráàyè máa fipá bá mi lò pọ̀'
Ohun ti Kate ko mọ ni pe oogun oorun lọkọ n ju sinuu tii fun un lalẹ, ki obinrin naa le sun, koun si le ba a sun rẹkẹrẹkẹ.

Ìdí tí ọ̀pọ̀ èèyàn káàkiri àgbáyé ṣe fẹ́ràn ìjọba ológun Burkina Faso
Ọpọ eeyan kaakiri agbaye lo gba ti Aarẹ ologun Ibrahim Traoré, amọ ki lo fa a?

Ìgalà fa ìjàmbá fún bàálù Air Peace, ó tún ṣàkóbá fún ìrìnàjò òfurufú ní Delta
Baalu yii ko le rin mọ lẹyin ti o kọlu ẹranko igbẹ naa tan lopopona rẹ ni papakọ ofurufu ilu Asaba.

Ìjàmbá tírélà ré kọ̀nténà lu ''dispatch rider' méjì l'Eko, wọ́n pàdánù ẹ̀mí wọn lójú ẹsẹ̀
Ẹka to n ri si ilanilọye nileeṣẹ to n ri si igbokegbodo ọkọ l’Ekoo, (LASTMA) fidi iṣẹlẹ ijamba naa mulẹ.

Ìdí tí ọlọ́pàá South Africa fi mú pásítọ̀ ọmọ Naijiria padà, lẹ́yìn tí iléẹjọ́ tú u sílẹ̀ lọ́gbà ẹ̀wọ̀n lórí ẹ̀sùn ìfipábánilòpọ̀
Gbogbo ẹsun onikoko mejilelọgbọn to da lori ifipabanilopọ, iyọnilẹnu fun ibalopọ ati ifiniṣowo ẹru ti wọn fi kan an ni adajọ naa yi danu ti o si paṣẹ pe ki o maa lọ ni alaafia.

Ǹjẹ́ ẹ ti gbọ́ nípa ìlú Ugbo nípìnlẹ̀ Ondo, níbi tó ti jẹ́ èèwọ̀ láti fẹ́ obìnrin pupa?
Olugbo tilẹ Ugbo, Ọba Akinruntan ni Moremi to dalẹ awọn Ugbo jẹ ọmọ pupa, to si tu asiri wọn fun Ile Ife, idi ree ti awọn Ugbo kii se fẹ obinrin pupa mọ.

Ta a ni eku ẹdá tó tún dá wàhálà sílẹ̀ lẹ́yìn tí India àti Pakistan gbà láti sinmi ogun?
Ikọ ologun awọn ilu mejeeji n fori gbari bayii ninu ija to ti le logun ọdun ti wọn bẹrẹ rẹ.

Femi Adebayo, Mercy Aigbe, fíìmù Lisabi, àti àwọn míì tó borí níbi àmì ẹ̀yẹ 2025 AMVCA
Ami ẹyẹ AMVCA ni wọn fi n mọ riri iṣẹ sinima nilẹ Africa

Ilé-ẹjọ́ ju ọmọge tó pé 'Bàbá Aláàánú' rẹ̀ lẹ́jọ́ sẹ́wọ̀n
Seyram lo pe ẹjọ tako Sugar Daddy rẹ, Ernest Kwasi Nimako pe o kun lati mu awọn ileri to ṣe fun wa si imuṣẹ.

Ohun tó yẹ kí o mọ̀ nípa ètò ìlera Medipool tí ìjọba ṣẹ̀ṣẹ̀ buwọ́lù fún aráàlú
Ijọba apapọ sọ pe ilana Medipool yii wa ni ibamu pẹlu ohun ti wọn n lo ni Kenya, South Africa, Singapore, ati Saudi Arabia.

Agbébọn kọlu ibùdó ọmọ ogun Naijiria, wọ́n jí ọ̀pọ̀ sọ́jà gbé lọ
Oṣojumi koro kan sọ fun awọn akọroyin pe awọn agbesunmọmi naa dana sun ọkọ ayẹta ileeṣẹ ọmọ ogun, wọn si ko ọpọ ohun ija oloro lọ nibẹ pẹlu.

Ìjọba UK kéde ìlànà tuntun tí yóò bẹ́gi dínà àwọn tó fẹ́ kàwé, ṣiṣẹ́ tàbí gbé níbẹ̀
Awọn ọmọ orilẹede Nigeria, Pakistan ati Sri Lanka wa lara awọn ti igbesẹ tuntun yii yoo pa lara julọ.

Àjọ NAPTIP kó ọmọ Naijiria 78 padà wálé lóko ẹrú láti Abidjan
Binta Adamu Bello, ọga agba NAPTIP to tẹwọ gba awọn eeyan naa, ṣeleri pe awọn to wa nidii iwa ifinisọko silẹ okeere lọna aitọ naa yoo koju ofin.

Kí ni ìdí abájọ tí Pásítọ̀ Chris fi sọ pé òun máa jẹ iyọ̀ tó pọ̀ nínú oúnjẹ?
Ileeṣẹ ijọba to n ri eto ilera ni iwadii fidi rẹ mulẹ pe ajẹju iyọ tawọn eeyan n jẹ lo n fa oriṣiiriiṣi aisan to n pa ẹgbẹẹgbẹrun eeyan lọdọọdun.

Sé lóòótọ́ làwọn agbégbọn kọ lẹ́tà pé àwọn tún fẹ́ kọlu ìjọ Aguda nílùú Owo? Ohun tí a mọ̀ rèé
Ti ẹ ko ba gbabe, ọjọ karun un, oṣu Kẹfa, ọdun 2022 lawọn agbebọn kan yabo ile ijọsin naa, nibi ti wọn to gbẹmi to le ni ogoji ti ọpo awọn mii si farapa.

'Mo ṣiṣẹ́ abẹ, wọ́n tún pàárọ̀ itan mi nítorí àìsàn ikọ́-ife inú egungun tó mú mi'
Lodi si ikọ hihu to maa n mu eeyan gbẹ ti a mọ ikọ-ife fun, ti inu egungun naa wa pẹlu iṣoro tirẹ.

Ìdí rèé tí iṣẹ́ ìtọ́jú èèyàn táwọn ọmọ ilẹ̀ òkèèrè ń ṣe ní UK yóò fi dópin láìpẹ́
Eeyan ti ko din ni 906,000 ni akọsilẹ fi han pe o wọle si UK lọdun 2023, nigba ti 728,000 wọ orilẹede naa lọdun 2024.

Wọ́n sọ iná sí ibùdó epo ní Port Sudan, aráàlú ń kérora
Ọjọ kẹfa lẹyin ti wọn lo drone kọlu wọn, eefin ina ṣi n ru jade lati ibudo epo mẹta ti wọn sọna si.

Wo ìrànlọ́wọ́ tó yẹ kí o ṣe fún ẹni tí rọpárọsẹ̀ bá kọlù lójijì
Bo ti wu ko kere to, akoko diẹ ti eeyan ba fi ṣofo ko too bẹrẹ itọju rọparọsẹ le di isọro nla, o si le fa iku ẹni ti aisan naa kọlu.

Bàbá Mohbad le pe ẹjọ́ tako ìdájọ́ tó tú Naira Marley àti Sam Larry sílẹ̀ - Ilé ẹjọ́
Baba Mohbad ní igbẹjọ to tu Naira Marley ati Sam Larry silẹ ko fun gbogbo awọn ti ọrọ naa kan lanfani lati wa sọ tẹnu wọn.

Local Housing

This is one of the main issues facing local people. The inadequacy of social housing stock continues to be the main concerns of local people. And it is getting worst.

Read More

Drugs And Illegal Substances

Taking illegal drug is always fraught with danger. You don't need me to tell you that - your grand mother will say the same. The high very often tend to perpetual low that you will never get out from. Get advise now before it is too late

Read More

Knife Attacks

Who goes around with a knive as weapon of protection is deluded. It will inevitably be your comeuppance. Just in case you do not understand, it will kill you. There is no justification for carrying a knive excerpt when you are foraging in the jungle.

Read More

Gang Culture

We were all young once - doing things adults will frown upon. This was at school or in the play grounds. But as we grew up, people we wanted to associate with start to shrink in numbers as our brain matured correspondingly and as a result doing the right thing. Pick your friends judiciously.

Read More

Local Parks

From a personal experience - the local park is a refuge for meditation,physical exploration and mental rejuvination. Just go for a slow run and see how you feel afterwards. Physical and mentally rewarding. Don't just take my words for it - it is a scientific fact. Please do try it.

Read More

24/7 Support

We are your one stop local solution advocate. Dont't carry all that weight on your own we are here to not only relief some of it, but to help you get back to you again.

Read More
Established since 2000

We Are Ready To Assist