Our Services



News From The BBC

A Yoruba Perspective


Igbákejì Gómìnà tẹ́lẹ̀rí Agboola Ajayi jáwé olúborí nínú ètò ìdìbò abẹ́lé PDP l'Ondo
Alaga igbimọ ẹlẹni meje to dari eto idibo naa nipinlẹ Ondo ti i ṣe Igbakeji Gomina Ipinlẹ Bayelsa, Sẹnẹtọ Ewhrudjakpo Oborawhartevwo lo kede Ajayi gẹgẹ bi ẹni to bori.

Ilé ẹjọ́ tó ga jùlọ kéde pé owó òṣù tí ìjọba ń san fún aya ààrẹ àti aya igbákejì ààrẹ lòdi sófin
Igbimọ adajọ ẹlẹni meje ti adajọ Gertrude Torkonoo dari rẹ fidi rẹ mulẹ pe ipo aya aarẹ ati aya igbakeji aarẹ kii ṣe ipo ọfiisi ijọba to tọ si owo oṣu gbigba.

Ọwọ́ ti tẹ mẹ́tàlá nínú àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sá lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Suleja - Mínísítà
Igbakeji adari ileeṣẹ ọgba ẹwọn lagbegbe FCT, AS Duza lo fidi iroyin naa mulẹ ninu atẹjade kan.

Kí ni El Niño àti La Niña, kí ní àjọṣepọ̀ wọn pẹ̀lú ojú ọjọ́?
El Niño ati La Niña, mejeeji yii jẹ ohun pataki si ayipada oju-ọjọ lagbaye.

Ẹ má kó oúnjẹ 5000 tí mo pín lọ sílé yín, àwọn mẹ̀kúnnù tó nílò rẹ̀ ni kí ẹ pín fún - Sanwo-Olu kìlọ̀
Ijọba Eko ni awọn eeyan ijọba ibilẹ ogun ati tawọn onidagbasoke (LCDA) mẹtadinlogoji to wa l’Ekoo ni yoo janfaani ounjẹ naa.

Bàbá mi kò lórúkọ́ àmọ́ èmi ti fòpin sí óṣèlú ‘ta a ni baba rẹ’ nipinlẹ Ọyọ - Ṣeyi Makinde
Ṣeyi Makinde ṣalaye pe igba kan ti wa ri nipinlẹ Ọyọ, to jẹ ta a ni baba tiẹ nilẹ yii ni wọn fi n se oṣelu.

Ọwọ́ ti tẹ mẹ́tàlá nínú àwọn ẹlẹ́wọ̀n tó sá lọ́gbà ẹ̀wọ̀n Suleja - Mínísítà
Igbakeji adari ileeṣẹ ọgba ẹwọn lagbegbe FCT, AS Duza lo fidi iroyin naa mulẹ ninu atẹjade kan.

Egypt ni Orunmila ti rìn wá, kìí ṣe Ile Ife, Ife kọ́ ni olùdáyé - Babaláwo
BBC Yorùbá bá Baba awo Obafemi Makinde sọ̀rọ̀ lórí Àtúpalẹ̀ ẹ̀sìn ifá, ẹni tó ṣàlàyé bí Orunmila ti ṣẹ̀ wá láti ilẹ̀ Egpty yàtọ̀ sí ilú Ile Ife tí ọ̀pọ̀ èèyàn rò pé ó jẹ́ Olùdáyé.

Àlàyé rèé lórí ìdí tí Amẹ́ríkà ṣe fẹ́ fòfin de TikTok
Aarẹ Amẹrika tẹlẹ ri, Donald Trump naa gbiyanju lọdun 2020 lati fofin de TikTok lasiko ijọba rẹ.

Mo ti bá olóòtú fíìmù lòpọ̀ rí, kí n lè kópa nínú sinimá rẹ̀ – Seun Sean Jimoh
Seun Sean Jimoh bo tilẹ jẹ pe iṣẹlẹ naa ti kuregbe-kuregbe, o ni o ṣi maa n ba oun ninu jẹ titi di oni yii.

Wàhálà míí tún bá Emefiele, EFCC ní odidi N18.9bn ló fi tẹ owó péréte N684.5m, òun yóò ba ṣe ẹjọ́ míì
Ọgbọnjọ oṣu Kẹrin ọdun yii ni Emefiele yoo foju ba ile ẹjọ niwaju adajọ Maryann Anenih ile ẹjọ giga ijọba apapọ niluu Abuja.

Ìdílé mùsùlùmí ẹlẹ́ni méje na ọmọbìnrin tó lọ ṣọ́ọ́ṣì ní pàsán ọgọ́rùn-ún, wọ́n dèrò àtìmọ́lé
Ọmọdebinrin kan ẹni ọdun mejidinlogun, Shakira Naula ni fidio naa se afihan rẹ pe Jaberi ati awọn eeyan kan n to ẹgba to to ọgọrun si nidi.

Multichoice kéde àfikún owó orí DStv, GOtv
Oṣu diẹ sẹyin ni afikun ṣi de ba owo ti awọn onibara n san fun mohunmaworan agbelewo DStv ati GOtv.

Ìjọba Nàìjíríà gbẹ́sẹ̀ lé iléeṣẹ́ bàlúù Dana Air
Lọjọ Iṣẹgun ni baluu Dana Air kan to fẹ ba ni papakọ ofurufu MMA ni ilu Eko yọ gẹrẹ kuro loju opo baluu ni papakọ ofurufu naa

Wàhálà míí tún bá Emefiele, EFCC ní odidi N18.9bn ló fi tẹ owó péréte N684.5m, òun yóò ba ṣe ẹjọ́ míì
Ọgbọnjọ oṣu Kẹrin ọdun yii ni Emefiele yoo foju ba ile ẹjọ niwaju adajọ Maryann Anenih ile ẹjọ giga ijọba apapọ niluu Abuja.

Àwọn àgbébọn kan fẹ́ jọ́wọ́ ohun ìjà wọn fún ìjọba láti kẹ̀yìn síwà ọ̀daràn – Ribadu
Ni ijọba ibilẹ Kankara, iṣoro eto abo tun ti n pada sawọn agbegbe kan nibẹ.

Bàbá, ọmọ àti aládùúgbò kú sí ṣálángá ni Kano
Ẹrọ ibanisọrọ Mallam Danjuma lo ṣeṣi ja si ṣalanga oniho naa nigba ti baba yii wa ninu ile igbọnsẹ ọhun, o si gbiyanju lati wọnu rẹ lọọ mu un.

Ọba Yoruba lórílẹ̀èdè Togo, Abdlkareem Afolabi Amon-lòkò wàjà
Wọn ti ṣeto isinku ori ade naa ni ilana ẹsin Musulumi.

Ọlọ́pàá yìnbọn pa ẹ̀gbọ́n tó wá bá àbúrò rẹ̀ yọ àyọ̀ ìkẹ́kọ̀jáde ní fásitì LAUTECH, èèyàn méjì míì farapa
Iroyin ni ọkan lara awọn oṣiṣẹ SARS, ti ijọba fopin si lọdun meji sẹyin ni ọlọpaa to yinbọ naa, eyii to ṣekupa agunbanirọ ti wọn pe orukọ rẹ ni Iyanda Damilola.

"Ẹ̀rù máa ń bà wá tẹ́lẹ̀ láti farahàn bíi oníṣẹ̀ṣe l‘Oyo, Ọba Adeyemi ló tì wá lẹ́yìn tí ìṣẹ̀ṣe kò fi di àtẹ̀mẹ́rẹ̀"
BBC Yorùbá wà ní ìlú Oyo fún ìrántí Aláàfin Lamidi Olayiwola Adeyemi tó wàjà lọ́dún méjì sẹ́yìn láti fojú ṣe mẹ́rin àwọn ètò ìrántí fún ọba tó dí olóògbé náà.

"Mo fi èèpo ẹ̀gẹ́ ṣe èlùbọ́ torí ọ̀dá owó fún àwa méje láti jẹ ọkà, ẹnìkan kú, àwa mẹ́fà dèrò ilé ìwòsàn"
BBC dé ìlú Ogbomoso níbi tí ọmọ kan ti kú lásìkò tí òun àti ẹbí rẹ̀ jẹ ọkà tí wọn fi èèpo ẹ̀gẹ́ ṣe, ìyá tó ro ọkà náà àti ọkọ rẹ̀ ṣàlàyé ìdí tí wọn fi ṣe bẹ́ẹ̀.

Olùdíje sípò gómìnà mẹ́ta kọ̀wé ẹ̀sùn kòtẹ́milọ́rùn sí Abuja lórí ètò ìbò abẹ́lé APC l'Ondo
Alaga igbimọ to dari eto idibo abẹle naa nipinlẹ Ondo, Gomina ipinlẹ Kogi, Ahmed Usman Ododo lo kede Lucky Aiyedatiwa gẹgẹ bi ẹni to bori.

Níbo lẹran màálú onímájèlé 50 kángun sí ní Ilorin lẹ́yìn tí ìjọba gbé ọjà ẹran Mandate tìpa?
Kọmisona feto ọgbin ni Ipinlẹ Kwara, Arabirin Thomas Adebayo ṣalaye pe, awọn ti lọ inu ọja naa lati ko awon ẹran naa.

Lẹ́yìn ọdún mẹ́wàá ní àhámọ́ ikọ̀ Boko Haram, wọ́n ṣàwárí akẹ́kọ̀ọ́ Chibok míì
Lydia tó fa ara rẹ̀ lé àwọn ẹ̀ṣọ́ ààbò náà lọ́wọ́ ní Gwoza ni wọ́n sọ pé ó wà nínú oyún oṣù márùn-ún àti pé láti ìlú Pemi ní Chibok ni òun ti wá.

Wo ilé ẹ̀kọ́ alákọ̀bẹ́rẹ̀ nílùú Eko tó ń gba N42m lórí ọmọ kan lọ́dún
Ọpọ ọmọ Naijiria lo ti n fi ẹhonu wọn han lori ayelujara lori owo gọbọi tawọn obi yoo maa san nile ẹkọ naa.

Ọkọ̀ ojú omi tó kó èèyàn 300 dojúdé ní Central African Republic, èèyàn 58 jáde láyé
Ẹnikan ti iṣẹlẹ naa ṣoju rẹ sọ fun ileeṣẹ iroyin RFI pe “iṣẹlẹ yii jẹ eyii to ba eeyan lẹru gidi.

Láti orí Fayoṣe dé Yahaya Bello, wo àwọn gómìnà tí wọ́n ti pitú fún EFCC rí
Eyi kọ lakọọko tawọn gomina yoo ti fọgbọn alumọkọrọyi japa mọ EFCC lọwọ, ti ajọ naa yoo si pada fọwọ ofin mu wọn.

Wo bí Meta ṣe fẹ́ fòpin sí gbígbà tábi fífi fọ́tò àti fídíò ìhòhò ránṣẹ́ lórí Instagram
Ileeṣẹ naa sọ pe oun maa lo imọ ijinlẹ lati mọ irufẹ atẹjiṣẹ DM to ni fọto tabi fidio ihoho.

Ilé aṣòfin Togo buwọ́lu òfin tí yóò mú kí Ààrẹ wà lórí oyè fún ọdún 26
Pẹlu ofin yii, Faure Gnassingbé yoo wa lori alefa titi di ọdun 2031.

Nǹkan tí ó le mú ọ̀wọ́ngógó oúnjẹ dínkù ní Nàìjíríà rèé - Ẹgbẹ́ àgbẹ̀
Dasaolu ni loootọ ni pe ọrọ aabo lo le ọpọ agbẹ kuro loko amọ to woye pe eto aabo Naijiria ti gbopọn si ju ti tẹlẹ lọ.

Báwo ni ohun ìjà olóró Iran ṣe lágbára tó sí ti Israel?
Ajọ International Institute for Strategic Studies (IISS) ṣapejuwe agbara awọn ohun ija oloro ileeṣẹ ologun orileede mejeeji yii nipa lilo ọrọ awọn agbẹnusọ, ati awọn miran to ṣee tọka si lati fi gbe abajade wọn sita.

Ìjọba ìpínlẹ̀ Oyo da ibùba àwọn ajìjàgbara Oodua Nation wò nílùú Ibadan
Bẹẹ ba gbagbe, awọn ikọ ajijagbara Oodua Nation yii lo kọlu ọgba ọfisi gomina ipinlẹ Oyo ati ile igbimọ aṣofin ipinlẹ Oyo ti wọn gbero lati gba ijọba

Wo ìgbésẹ̀ tí Toyin Abraham gbé bí ìjà láti di ẹni àkọ́kọ́ lágbo tíátà ṣe ń wáyé láàrín àwọn òṣèré
Abraham ni asiko ti to fun awọn lati gbe ara wọn lárugẹ, ki wọn si yago fun kikorira ara wọn tabi fífi ẹgbẹkẹgbẹ ni ọna ti ko ni alaafia.

Akintoye àti Igboho ń sọ tiwọn ni, àtúntò ni a dúró fún – Afenifere
Lẹta ọhun, ti wọn kọ lọjọ kẹtadinlogun, oṣu Kẹrin, ọdun 2024 yii ni Akintoye, Igboho ati Ola Ademola buwọlu.

Àwọn agbébọn kọlu baálè méjì l’Ogun, wọ́n pa ẹ̀ṣọ́ aláàbò kan
O ṣoju mi koro kan ti ko darukọ rẹ, sọ pe ori ati ejika ni ibọn ti ba awọn baalẹ naa.

Olùdíje sípò gómìnà mẹ́ta kọ̀wé ẹ̀sùn kòtẹ́milọ́rùn sí Abuja lórí ètò ìbò abẹ́lé APC l'Ondo
Alaga igbimọ to dari eto idibo abẹle naa nipinlẹ Ondo, Gomina ipinlẹ Kogi, Ahmed Usman Ododo lo kede Lucky Aiyedatiwa gẹgẹ bi ẹni to bori.

Kóótù gba onídùúró Cubana Chief Priest pẹ̀lú mílíọnù mẹ́wàá náírà
Bi ẹ ko ba gbagbe, laipẹ yii ni ile-ẹjọ giga apapọ ju Bobrisky sẹwọn oṣu mẹfa gbako pẹlu iṣẹ aṣekara lai fi aye silẹ fun owo itanran rara.

Ọdún ọmọ ìlú Ìbarà bẹ̀rẹ̀ l’Abẹ́òkúta lákọ̀tun
Ẹẹkan ṣoṣo laarin ọdun mẹta ni ayẹyẹ Ọdun ọmọ Ibara maa n waye, nibi ti wọn ti maa n ṣafihan awọn ohun iṣẹmbaye wọn bii Yemọja, Ẹfẹ ati Gẹlẹdẹ, gẹgẹ bi a ṣe gbọ.

Israel ju àdó olóró sí àárín gbùngbùn Iran, ariwo sọ
Iran la gbọ pe wọn ti gbaradi gidi nigba ti awọn Israel sọ pe awọn yoo gbẹsan ikọlu ti awọn ara Iran ṣe si wọn lọjọ Abamẹta to kọja.

Àwọn agbébọn yawọ abúlé, jí àwọn obìnrin àti àwọn ọmọ gbe ní Katsina
Iṣẹlẹ yii ti sọ ọpọ awọn to n gbe lagbegbe naa di alainile lori ati ẹru awọn ajinigbe.

Bíṣọ́ọ̀bù tí wọ́n gún lọ́bẹ lóun ti dáríji àwọn tó kọlu oun
Ileeṣẹ ọlọpaa to fidi ikọlu ọhun mulẹ fawọn akọroyin sọ pe awọn agbebọn lo ṣe ikọlu naa, ti wọn si ṣe ọpọ awọn olujọsin, to fi mọ awọn olori ijọ leṣe.

'Orí ló kó mi yọ lọ́wọ́ ikú, àwọn ọ̀rẹ́ mi mẹ́rin ni wọ́n pa'
Ó ní ohun ìyàlẹ́nu ló jẹ́ fún òun pé òun móríbọ́ àti pé òun kàn farapa níbi èjìkà lásán ni.

Ọ̀rọ̀ epo pupa dá wáhàlá láàrin ìyá àti ọmọ rẹ̀ l'Osun, ẹ̀mí ìyá bọ́ síi
Nigba to fi idi iṣẹlẹ naa fun BBC News Yoruba, agbenusọ ọlọpaa ipinlẹ Osun, Yemisi Opalola ni iwadii ti bẹrẹ lati mọ ohun to ṣokunfa aawọ naa.

Ilé ẹjọ́ buwọ́lu ìyọ̀nípò Ganduje, ariwo sọ
Ẹsun siṣe owo ilu mọkumọku ni wọn fikan Ganduje

Local Housing

This is one of the main issues facing local people. The inadequacy of social housing stock continues to be the main concerns of local people. And it is getting worst.

Read More

Drugs And Illegal Substances

Taking illegal drug is always fraught with danger. You don't need me to tell you that - your grand mother will say the same. The high very often tend to perpetual low that you will never get out from. Get advise now before it is too late

Read More

Knife Attacks

Who goes around with a knive as weapon of protection is deluded. It will inevitably be your comeuppance. Just in case you do not understand, it will kill you. There is no justification for carrying a knive excerpt when you are foraging in the jungle.

Read More

Gang Culture

We were all young once - doing things adults will frown upon. This was at school or in the play grounds. But as we grew up, people we wanted to associate with start to shrink in numbers as our brain matured correspondingly and as a result doing the right thing. Pick your friends judiciously.

Read More

Local Parks

From a personal experience - the local park is a refuge for meditation,physical exploration and mental rejuvination. Just go for a slow run and see how you feel afterwards. Physical and mentally rewarding. Don't just take my words for it - it is a scientific fact. Please do try it.

Read More

24/7 Support

We are your one stop local solution advocate. Dont't carry all that weight on your own we are here to not only relief some of it, but to help you get back to you again.

Read More
Established since 2000

We Are Ready To Assist